Font Size
Deuteronomi 32:6
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Deuteronomi 32:6
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
6 Ṣé báyìí ni ẹ̀yin yóò ṣe san an fún Olúwa,
Háà, ẹ̀yin aṣiwèrè àti aláìgbọ́n ènìyàn?
Ǹjẹ́ òun kọ́ ni baba yín, Ẹlẹ́dàá yín,
tí ó dá a yín tí ó sì mọ yín?
Isaiah 63:16
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Isaiah 63:16
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
16 Ṣùgbọ́n ìwọ ni baba wa,
bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé Abrahamu kò mọ̀ wá
tàbí Israẹli mọ ẹni tí à á ṣe;
ìwọ, Olúwa ni Baba wa,
Olùràpadà wa láti ìgbà n nì ni orúkọ rẹ.
Isaiah 64:8
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Isaiah 64:8
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
8 Síbẹ̀síbẹ̀, Olúwa, ìwọ ni Baba wa.
Àwa ni amọ̀, ìwọ ni amọ̀kòkò;
gbogbo wa jẹ́ iṣẹ́ ọwọ́ rẹ.
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn (BYO)
Copyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.