Amosi 1:4
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
4 Èmi yóò rán iná sí ilé Hasaeli
Èyí ti yóò jó àwọn ààfin Beni-Hadadi run.
Amosi 1:7
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
7 Èmi yóò rán iná sí ara odi Gasa
tí yóò jó gbogbo ààfin rẹ̀ run
Amosi 1:10
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
10 Èmi yóò rán iná sí ara odi Tire
Tí yóò jó gbogbo àwọn ààfin rẹ̀ run.”
Amosi 1:12
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
12 Èmi yóò rán iná sí orí Temani
Tí yóò jó gbogbo ààfin Bosra run.”
Amosi 1:14
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
14 Èmi yóò rán iná sí ara odi Rabba
èyí tí yóò jó àwọn ààfin rẹ̀ run
pẹ̀lú ìhó ayọ̀ ní ọjọ́ ogun,
pẹ̀lú ìjì líle ni ọjọ́ àjà.
Amosi 2:2
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
2 Èmi yóò rán iná sí orí Moabu
èyí tí yóò jó àwọn ààfin Kerioti run.
Moabu yóò sì kú pẹ̀lú ariwo
pẹ̀lú igbe àti pẹ̀lú ìró ìpè
Amosi 2:5
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
5 Èmi yóò rán iná sí orí Juda
èyí tí yóò jó àwọn ààfin Jerusalẹmu run.”
Copyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.