Font Size
Marku 9:50
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Marku 9:50
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
50 (A)“Iyọ̀ dára, ṣùgbọ́n tí ó bá sọ adùn rẹ̀ nù, báwo ni ẹ ṣè lè padà mú un dùn? Ẹ ni iyọ̀ nínú ara yín, ki ẹ sì máa gbé ní àlàáfíà pẹ̀lú ara yín.”
Read full chapter
Romu 12:18
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Romu 12:18
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
18 (A)Bí ó bá sé é ṣe, bí ó ti wà ní ipa tiyín, ẹ má wà ní àlàáfíà pẹ̀lú gbogbo ènìyàn.
Read full chapter
1 Tẹsalonika 5:11
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
1 Tẹsalonika 5:11
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
11 Nítorí náà, ẹ máa gba ara yín níyànjú, kí ẹ sì máa gbé ara yín ró, gẹ́gẹ́ bí ẹ ti ń ṣe.
Read full chapter
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn (BYO)
Copyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.